Nibi isinku Kayode Esho, Gomina Aregbesola ro eka idajo

Transkript

Nibi isinku Kayode Esho, Gomina Aregbesola ro eka idajo
E ba wa dele
E mo nipa wa
E polowo oja yin
AKEDE Agbaye
Idanileko ALAROYE
Bi o ba fe ba wa sise
Adiresi wa
Nibi isinku Kayode Esho, Gomina Aregbesola ro eka idajo lati maa
sagbekale idajo nilana ofin
Awon Iroyin to se koko
Bisi Adesoye, Ilesa
Fayose derin-in peeke
G
awon olokada l’Ekiti
omina
ipinleô
O·sôun,
O·gbeôni
Rauf
Adesoôji
Areôgbeôsôoôla gbosôuba fun
Oloogbe Onidajoô Kayoôde
Eôshoô geôgeô bii eôni to jeô
olotitoô, oômoôluabi ati eôni to
mu eto idajoô goke agba ni
orileô-ede
yii. O·gbeôni
Areôgbeôsôoôla soôroô yii di mimoô
nibi ayeôyeô eto isinku oloogbe
naa to waye n’Ileôsôa, loôjoô Eôti,
Abiola Ajimobi tipinle Oyo, igbakeji Gomina ipinle Osun, Arabinrin Titilayo
Fraide, oôseô to koôja.
Laoye-Tomori, Iyawo Oloogbe Onidajo Kayode Esho, Helena, ati aburo
Ninu oôroô Gomina lo ti roô
Oloogbe, Eni-Owo Ladipo Esho, nibi apejo pataki ti won se fun Oloogbe ni
kootu giga tilu Ibadan
gbogbo awoôn ti woôn wa leôka
idajoô lorileô-ede yii pata lati ri
oloogbe yii geôgeô bii awokoôsôe eeyan kan to duro lori lilo ofin ninu idajoô reô. Oni gbogbo idajoô
Oloogbe Eôshoô lo jeô ohun to sôe e toôkasi fawoôn agbeôjoôro gbogbo to wa ni lorileô ede yii, nitori
gbogbo reô lo jeô eyi to gbekaleô loôna ofin.
Nigba ti Bisôoôoôbu eôkun Ilesôa,Rt. Rev Dr. Olubayoô Sôowale, n soôroô nibi iboji oloogbe naa lo ti
soô pe Oloogbe Kayoôde Eôshoô jeô onigbagboô eeyan ti ko ko ohun aye maya. Oni ijoô Anglican
ko ni i gbagbe reô nipa bo sôe fi ile ijoôsin to koô sinu oôgba ile reô lopopona Oke-Omiru, Ilesôa, ta
ijoô naa loôreô. Bakan naa ni asôiwaju ijoô naa soô pe ipa ribiribi ti Onidajoô yii ti ko laye, ati bo sôe
sôe beôbeô ninu isôeô to yan laayo ni ko ni i jeô ki awoôn eeyan gbagbe eô laelae.
Ninu oôroô isôiri ti Bisoôoôbu ba awoôn eeyan soô loôjoô naa lo ti roô gbogbo awoôn ti woôn wa ni ilana
eto idajoô atawoôn agbeôjoôro pata lati ma sôe jeô ki ilana ti oloogbe fi leleô pareô, paapaa juloô nipa
eto idajoô ati ti eôka agbeôjoôro lorileô-ede yii.
Lasiko tawoôn oômoô meji ti oloogbe yii fi sileô n bu eeru fun eeru, erupeô fun erupeô ni omije n
jade loju woôn, iyawo reô ati
oôgoôoôroô awoôn eeyan ni woôn si peju seti iboji lati sôe eôyeô ikeôyin fun un.
Iduunu subu layo
fawon osise nipinle
Oyo, orisiirisii ajemonu
nijoba fun won
Eto eko nijoba yoo
nawo le lori julo lodun
to n bo nipinle Kwara
N’Ilesa, won fesun
agbere kan pasito, lo ba
ni ise esu ni, o ti foju
bale-ejo
Owo awon eleto aabo
ilu te awon to n ji epo
bentiroolu wa nipinle
Ogun
Keshi gbe oruko awon
agbaboolu jade fun
idije Nations Cup
E tun pade wa lori ero
E wa awon iroyin wa